ILÉ ÌGBÌMỌ̀ AṢÒFIN ÌPÍNLẸ̀ ÈKÓ: ÌDÚPẸ́

Olùdarí, Aṣòfin Mudashiru Àjàyí Ọbásá, àwọn Olóyè Ilé, Ọmọ-ẹgbẹ́ Aṣòfin, Àwọn Alákòóso àti Òṣìṣẹ́ Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Ìpínlẹ̀ Èkó dúpẹ́ púpọ̀ lọ́wọ gbogbo àwọn Gómìnà, Ọba Alayélúwà, Ọ̀tọ̀kùlú àti àwọn ẹni bí ẹni tí a pè tí wọ́n jẹ́ ìpè wá ní àsìkò Ìpàdé Àwọn Alẹ́nulọ́rọ̀ tí a ṣe ní Ọjọ́bọ, Ọjọ́ Kejì oṣù Kẹfà, ọdún Ẹgbàálémẹ́ríndínlógún pẹ̀lú àkọ́lé: “Mímú Ẹ̀kọ́ Èdè Yorùbá Ní Kàn-ń-pá Ní Àwọn Iléèwé Ìjọba Àti Aládàáni Ní Ìpínlẹ̀ Èkó.”

A gbé òṣùbà ràbàǹdà fún un yín fún àtìlẹ́yìn, àmọ̀ràn àti ipa ribiribi tí ẹ kó ní àsìkò ètò náà.

Ní pàtàkì jùlọ, ọpẹ́ àtinúwá wa lọ sí ọ̀dọ àwọn ènìyàn jàn-ǹ-kàn jàn-ǹ-kàn wọ̀nyí:

ü Ọlọ́lá-jùlọ Ọ̀gbẹ́ni Rauf Adésọjì Arẹ́gbẹ́ṣọlá (Gómìnà ti Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun)

 

ü Ọba Ẹnìtán Adéyẹyè Ògúnwùsì (Ọ̀ọ̀ni ti Ilẹ̀ Ifẹ̀)

 

ü Baṣọ̀run Muyiwa Ọládiípọ̀ (Aṣojú Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ògùn)

 

ü Àwọn Ọmọ-ẹgbẹ́ Aṣòfin Ìpínlẹ̀ Ògùn àti Ọ̀ṣun

 

ü Aṣòfin Jókòtọ́lá Pẹ̀lúmi (Olùdarí tẹ́lẹ̀ rí ní Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Ìpínlẹ̀ Èkó)

 

ü Àwọn Ọmọ-ẹgbẹ́ Aṣòfin tẹ́lẹ̀ rí ní Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Ìpínlẹ̀ Èkó

 

ü Aṣòfin-àgbà Ọlọ́runḿbẹ Mamora

 

ü Alága àti àwọn Kọmíṣánnà Ìgbìmọ̀ Amójútó Ọ̀rọ̀ àwọn Òṣìṣẹ́ Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Ìpínlẹ̀ Èkó

 

ü Ọ̀jọ̀gbọ́n Àkànní Igue

 

ü Alàgbà Peter Fátómilọ́lá

 

ü Ọ̀jọ̀gbọ́n Olú Akéwúṣọlá

 

ü Ọ̀jọ̀gbọ́n Orímóògùnjẹ́

 

ü Ọ̀gbẹ́ni Olúṣọlá Macaulay (Aṣojú Àjọ UNESCO)

 

ü Àwọn Olóyè Onífìlà Funfun

 

ü Olóyè Ìdòwú Ọbásá

 

ü Lánre Aya Hassan

 

ü Ẹgbẹ́ Ìgbìmọ̀ Ọ̀dọ́ Ilẹ̀ Yorùbá

 

ü Iléeṣẹ́ Aṣèwétà Aqua Green Limited

 

ü Gbogbo Ọ̀jọ̀gbọ́n, Ọ̀mọ̀wé, Iléeṣẹ́, Oníròyìn,   Akẹ́kọ̀ọ́, àti ènìyàn àtàtà yòókù tí a ò dárúkọ.

 

 

ü Ọlọ́lá-jùlọ, Bọ́láńlé Aya Aḿbọ̀dé (Aya Gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkó)

 

ü Ọba Làmídì Adéyẹmí (Aláàfin ti Ìlú Ọ̀yọ́)

 

ü Aṣòfin Suraj Ìṣọ̀lá Adékúnbi (Olùdarí, Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Ìpínlẹ̀ Ògùn)

 

ü Dókítà Samuel Adéjàre (Kọmíṣánnà Ètò Àyíká ní Ìpínlẹ̀  Èkó)

ü Ọ̀gbẹ́ni Kehinde Joseph (Olùdámọ̀ràn Pàtàkì sí Gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkó lóri Ọ̀rọ̀ Ìdásí Aráàlú)

 

ü Àwọn Ọmọ-ẹgbẹ́ Akọ̀wé-àgbà àti Olùkọ́ni-àgbà ní Ìpínlẹ̀ Èkó

 

ü  Aṣòfin Àbáyọ̀mí Kínyọmí

 

ü Aláíge ti Orílé Agége

 

ü Àlájì Mùtíù Àrẹ

 

ü Ọ̀jọ̀gbọ́n Akínwùmí Ìṣọ̀lá

 

ü Ọ̀jọ̀gbọ́n Adéníyì Harrison

 

ü Ọ̀jọ̀gbọ́n Akinloyè Òjó (Yunifásitì ti Georgia)

 

ü Ọ̀jọ̀gbọ́n Fákinlèdé K.J.

 

ü Ọ̀jọ́gbọ́n Ajíbóyè O.J.

 

ü Ọ̀mọ̀wé Ìlọ̀rí J.F.

 

ü Aṣojú Àjọ UNICEF

 

ü Àwọn Alága Ìjọba Ìbílẹ̀ àti Agbègbè Ìdàgbàsókè Ìjọba Ìbílẹ̀ ní Ìpínlẹ̀ Èkó

 

ü Alàgbà Túndé Kèlání

 

ü Àwọn Báálẹ̀ láti Ìjọba Ìbílẹ̀ Agége

 

 

 

ü  Ọlọ́lá-jùlọ, Ọ̀mọ̀wé Olúrántí Adébùlé (Igbákejì Gómìnà Ìpínlẹ̀ Èkó)

 

ü  Ọba Rilwan Àrẹ̀mú Akiolú (Ọba ti Ìlú Èkó)

 

ü  Aṣojú Alága Ẹgbẹ́ Òṣèlú APC ní Ìpínlẹ̀  Èkó

 

ü  Aṣòfin-àgbà Ọlábìyì Dúrójayé

 

ü  Aṣòfin Ọláwálé Oshun

 

ü  Ọba Kàbírù Agbábíàká (Ọsọ́lọ̀ ti Ìsọlọ̀)

 

ü  Àlájì S.A. Sùnmọ́là

 

ü  Falilat Aya Ọbásá àti gbogbo àwọn Aya Aṣòfin Ìpínlẹ̀ Èkó

 

ü  Ọ̀jọ̀gbọ́n Dúró Adélékè

 

ü  Ọ̀jọ̀gbọ́n Sophie Olúwọlé

 

ü  Àlájì  Kareem Adépọ̀jù

 

ü  Ọ̀jọ̀gbọ́n Dípọ̀ Gbénró

 

ü  Ọ̀jọ̀gbọ́n Abísógun Leigh

 

ü  Ọ̀mọ̀wé Oyèwálé A.S.

 

ü  Àwọn Alákòóso láti Iléeṣẹ́ Ìjọba àti Iléeṣẹ́ Aṣojú Ìjọba

 

ü  Ọmọọba Jídé Kòsọ́kọ́

 

ü  Ọ̀túnba Adébáyọ̀ Sàlámì

 

ü  Ẹgbẹ́ àwọn Akọ́mọlédè àti Àṣà Yorùbá

 

ü  Ilé Ìfowópamọ́ WEMA

 

ü  Iléeṣẹ́ Aṣèwétà Learn Africa

 

ü Ẹgbẹ́ àwọn Olùkọ́-àgbà ní Iléèwé Sẹ́kọ́ǹdìrì ní Ìpínlẹ̀ Èkó

 

 

Ẹ ṢÉ PÚPỌ̀. OÒDUÀ Á GBÈ WÁ O!

 

 

 

 

 

 

 

 

 

 

 

 

 

 

         

AṢÒFIN MUDASHIRU ÀJÀYÍ ỌBÁSÁ     

OLÙDARÍ, ILÉ ÌGBÌMỌ̀ AṢÒFIN ÌPÍNLẸ̀ ÈKÓ

 

 

 

 

 ILÉ ÌGBÌMỌ̀ AṢÒFIN ÌPÍNLẸ̀ ÈKÓ………………………………………..………ó tayọ ìgbéléwọ̀n àṣeyọrí.

 

Write a Comment

Your email address will not be published. Required fields are marked *